Àjíǹde: Adarí ilé, Igbákejì rọ àwọn kírísítíẹ́nì láti kọ́ ìṣe kŕisítì
Adarí ilé ìgbìmọ̀ Aṣojú, ọ̀gbẹ́ni Abbas Tajudeen àti igbákejì rẹ̀ Benjamin Kalu ti rọ àwọn ọmọ lẹ́yìn kírísítí láti kọ́ ìṣe ìfaradà Jésù Kírísítì.
Wọn rọ awọn ọmọ Naijiria lati ni ifẹ ara wọn lai bikita ẹya, ẹsin,…