Ààrẹ Tinubu ṣèpàdé pẹ̀lú Adarí Ìṣọ̀kan àwọn orílẹ̀-èdè Adúláwọ̀
Ààrẹ Bola Ahmed Tinubu gbàlejò Adarí Ìṣọ̀kan àwọn orílẹ̀-èdè Adúláwọ̀ (AFRICOM), Ajagun Dagvin Anderson, ní ọjọ́ Aiku ní ilé isẹ́ orílẹ-èdè, Abuja.
Àwọn ti o wà nijokoo nibi ipade naa ni Oludamọran lori ọrọ aabo…