Aṣòfin gbóríyìn fún ààrẹ Tinubu lórí ìpèsè àfikún owó iṣé fúngbà díẹ̀
Ọmọ ilé ìgbìmọ̀ asojú ṣòfin kan, Dókítà Ahmed Aluko ti gbóríyìn fún ìjọba Nàìjíríà fún bí ó ṣe fi ẹgbẹ̀rún márùnlé-lọ́gbọ̀n Náírà kún owó oṣù àwọn òṣìṣẹ́ ìjọba fún oṣù mẹ́fà.
Aṣofin ti n ṣoju iwọ…