Kòsí Ìgbàláyè Fún Ọkọ̀ Akérò Pẹ̀lú Ọ̀dà Ayédèrú Láti Sisẹ́ Ní Abuja- Nyesom Wike
Mínísítà Ìlú Abuja, Ọ̀gbẹ́ni Nyesom Wike sọ pé ìjọba yóò fi òfin de àwọn ọkọ̀ akérò tí kò ní ọ̀dà tí ìjọba fi ọwọ́ fí láti siṣẹ́ ní òpópónà gbogbo ní ìlú Abuja
Wike síṣọ lójú ọ̀rọ̀ náà nígbà…