Take a fresh look at your lifestyle.

Nàìjíríà Tí Bẹ̀rẹ̀ Ìsinmi Ìbímọ Fún Àwọn Òṣìṣẹ́ Ìjọba Ọkùnrin

Ìjọba orílẹ̀-èdè Nàìjíríà tí bẹ̀rẹ ìsinmi lẹnu iṣẹ́ ọlọjọ mẹrinla fún àwọn ọkùnrin òṣìṣẹ́ ìjọba tí ìyàwó wọn bímọ. Èyí ní yóò bẹ̀rẹ̀ gẹ́gẹ́bí àkọlé ìwé àwọn òṣìṣẹ́ tí wọ́n pé àkọlé rẹ̀ ní "àkọsílẹ̀ ọjọ́ ìsinmi lẹ́nu ìṣẹ́ àwọn òṣìṣẹ́…

Ẹgbẹ́ Àgbábọ́ọ̀lù Orílẹ̀-èdè Faransé Tí Bú Ẹnu Àtẹ Lù Bí Àwọn Kàn Ṣé Ń Takò Orílẹ̀-èdè Qatar Làpọ̀jù

Alàkóso àgbábọ́ọ̀lù Faransé (FFF) Noël Le Graët tí gbà láti dáàbòbo Qatar gẹ́gẹ́ bí àgbàlejo tí ìdíje Ife Àgbáyé 2022. "Mó gbàgbọ́ pé ìpolongo itako náà tí pọ̀jù fún Qatar. Ní tòótọ, a n'ifẹ látí máà ṣé àṣejù díẹ̀ ní Ìlú Faransé…

Àtúntẹ̀ Owó Náírà: Ilé Ifowopamọ Àpapọ̀ Yóò Ríi Dájú Pé Ètò Ọrọ Àjé Tí Kò Ní Òwó Nínú Ṣiṣẹ́

Gómìnà tí ilé ifowopamọ àpapọ̀ (Central Bank of Nigeria CBN), Godwin Emefiele sọ pé pẹ̀lú iṣafihan àwọn àtúntẹ̀ owó náírà ilé ifowopamọ yóò ríi dájú pé ètò ọrọ̀ ajé tí kò ní ṣé pẹ̀lú owó gbígbé kà yóò di dandan ní gbogbo orílẹ̀-èdè náà.…

A Ṣé Àtúntẹ̀ Owó Wà Látí Ṣé Ìṣàkóso Tó Péye Lórí Rẹ̀ – Ààrẹ Buhari

Ààrẹ Muhammadu Buhari sọ pé ìpinnu látí ṣé àtúntẹ̀ àwọn owó Náírà kàn jẹ́ láti kojú ìwúlò ati ìṣàkóso rẹ̀ ní kíkún, ààbò àwọn owó bánkì, idinku àwọn ayédèrú, titọju àwọn ohun-ìní tí ìjọba àpapọ̀ àti idinku àpapọ̀ ìyè owó tó wà ní àwùjọ.…

Nàìjíríà Yóò Só Àwọn Olú-ìlú Ìpínlẹ̀ Pọ̀ Pẹ̀lú Ọkọ̀ Ojú-irin Tó Múná Dóko

Mínísítà fún ètò irinna lórílẹ̀ èdè Nàìjíríà, Mu’azu Sambo tí fí dá àwọn ọmọ orílẹ̀-èdè Nàìjíríà lójú pé ètò ojú-irin tuntun yóò só gbogbo olú-ìlú ìpínlẹ̀ Nàìjíríà pọ̀. Ọgbẹni Sambo ṣé ìdánilójú náà làkókò tó n sọ ọ̀rọ̀ níbí ayẹyẹ Ogún…
button