Take a fresh look at your lifestyle.

Yíyọ Owó-Ìrànwọ́ Orí Èpò Kúrò: Ijọba Nàìjíríà Ṣé ìdánilójú Ètò Ìrọrùn

Alága, Àjọ ètò ìrọrùn lórí yíyọ ìrànwọ́ orí èpò kúrò "Palliative Committee on Subsidy Removal" àtí Gómìnà Ìpínlẹ̀ Kebbi, Dókítà Nasir Idris, tí fí dá àwọn ọmọ orílẹ̀-èdè Nàìjíríà lójú pé àwọn tí bẹ̀rẹ̀ ìgbìyànjú lójúnà látí ṣé ìdẹ́kun lórí…

Ilé-ìgbìmọ̀ Aṣòfin Nàìjíríà Ṣetân Láti Ṣé Àyẹwò Fún Àwọn Olórí Iṣẹ́ Ààbò Túntún

Ilé-ìgbìmọ̀ aṣòfin Nàìjíríà tí ṣetán bayi látí ṣé àyẹ̀wò kí wọ́n sì buwọ́lù iṣẹ́ àwọn Olórí ìṣẹ́ ààbò túntún tí orílẹ̀-èdè yìí, ní atẹle sí ìbéèrè tí Ààrẹ Tinubu. Ìbéèrè tí Ààrẹ Tinubu náà wà nínú lẹta tó kọ sí Ààrẹ Ilé-ìgbìmọ̀ aṣòfin…

Àwọn Aṣòfin Rọ́ Ilé Ìfówópámọ́ Àpapọ̀ Látí Ṣé Sùúrù Lórí Àbàdófin Kàn

Ilé-ìgbìmọ̀ Aṣojú Ṣòfin tí rọ́ Bánkì Àpapọ̀ Nàìjíríà CBN, látí ṣé ìdádúró sí àbàdófin "Mọ́ Oníbárà Rẹ̀." Èyí ló wáyé lẹyìn àbàdófin tí ọmọ ẹgbẹ́ Ilé-ìgbìmọ̀ aṣòfin kàn látí ìpínlẹ̀ Rivers, Ọ̀gbẹ́ni Kelechi Nwogu Ọ̀gbẹ́ni Nwogu…

Nàìjíríà Ṣé Tàn Láti Gbé Gáàsì Kọjá Lọ́ Sí Ìwọ̀ Oòrùn Áfíríkà Títí Dé Yúróòpù

Ilé-iṣẹ́ ìfọ́pó orílẹ̀-èdè Nàìjíríà "Nigeria National Petroleum Company Limited NNPCL" sọ pé o tí ṣé tàn látí gbé gáàsì kọjá lọ́ sí ìwọ̀ òòrùn Áfríkà títí dé Yúróòpù. Olùdarí àtí Aláṣẹ tí ẹgbẹ́ NNPC, Mele Kolo Kyari sọ èyí nígbà tó ń…
button