Àyá Ààrẹ Nàìjíríà Bú Ọlá Fún Àwọn Tó Pàdánù Ẹ̀mí Wọ́n Nínú Ikọlù Ilé-iṣẹ́ UN
Ìyàwó Ààrẹ Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà, Oluremi Tinubu tí gbé oríyìn fún àwọn aráàlú tí wọ́n pàdánù ẹ̀mí wọ́n nínú ìkọlù bọ́ǹbù tí Ilé-iṣẹ́ Àjọ Àgbáyé 'United Nations' ní ìlú Abuja ní ọjọ́ kẹrindinlọgbọn Oṣù Kẹjọ Ọdún 2011.
Nígbà tó n sọ̀rọ̀…