Take a fresh look at your lifestyle.

Ẹ̀ka Ilé-iṣẹ́ Mọ̀nàmọ́ná Nàìjíríà Ló Ṣé Pàtàkì Jù Fún Ìdàgbàsókè Ètò Ọ̀rọ̀-ajé – Mínísítà

Mínísítà fún ètò Iná Mọ̀nàmọ́ná Nàìjíríà, Adebayo Adelabu tí ṣé àpèjúwe ẹ̀ka náà gẹ́gẹ́ bí èyí tó ṣé pàtàkì jùlọ lorílẹ̀-èdè yí fún ìdàgbàsókè ètò ọrọ̀-ajé àti ìdàgbàsókè àwọn ilé-iṣẹ́. Mínísítà náà sọ èyí ní ìlú Abuja nígbà tó ń bá…

Àwọn Aṣojú Orílẹ̀-èdè Bù Ẹnú Atẹ́ Lù Ipaniyan Tó Ṣẹ̀lẹ̀ Ní Ìpínlẹ̀ Èkó

Ilé ìgbìmọ̀ aṣòfin tí bú ẹnú àtẹ lú ìwà-ipá, ipaniyan, ihamọ àti ikọlù tí ọlọ́pàá lórí àwọn ènìyàn Oshodi Isolo Federal Constituency II, ní ìpínlẹ̀ Èkó, Nàìjíríà. Ilé náà tún ke sí Ọgá Ọlọ́pàá Gbogbogbò (IGP) láti bẹ̀rẹ̀ ìwádìí ní…

Mínísítà Ṣé Ìlérí Àtìlẹ́yìn Fún Ètò Ọmọnìyàn Àtí Ile-Òṣì-Wọ́lẹ̀

Mínísítà fún Ìròyìn àti Àlàyé tí orílẹ̀-èdè Nàìjíríà, Mohammed Idrsi sọ pé ilé-iṣé rẹ̀ yóò ṣé àtìlẹ́yìn àti ìfọwọ́sowọ́pọ̀ iṣẹ́ àti àwọn ètò tí Ilé-iṣẹ́ Ọmọnìyàn àti ilé-òṣì-wọ́lẹ̀ gẹ́gẹ́ bí ìgbìyànjú láti ṣaṣeyọri èròngbà Ààrẹ (8-Point…
button