Take a fresh look at your lifestyle.

Agbẹnusọ Ilé-ìgbìmọ̀ Aṣojú Ṣofin Npé Àwọn Mùsùlùmí Láti Ṣé Igbelarugẹ Ìfẹ Àti Ìṣọ̀kan

Agbẹnusọ ilé ìgbìmọ̀ Aṣojú-ṣofin, Femi Gbajabiamila tí pe awon Mùsùlùmí láti ṣé àmúlò ìwà àti ẹkọ Anabi Muhammad (SAW) nínú àjọṣepọ̀ wọ́n pẹ̀lú Ọlọrun àti ẹdá ènìyàn. Èyí wáyé gẹ́gẹ́ bí ọrọ rẹ sí àwọn mùsùlùmí nígbà tí wọ́n ń ṣé ayẹyẹ…

Ìgbìmọ̀ Àwọn Aláṣẹ Orílẹ-èdè Nàìjíríà Gbà Ètò Ìṣúná 2023 Tí Ìlé-ìṣẹ́ Ààrẹ Gbekalẹ Wọlé

Ìgbìmọ̀ Aláṣẹ tí orílẹ-èdè yìí tí fọwọ́sí ìmọràn ìṣúná 2023 láti fí ṣọwọ́ sí ilé ìgbìmọ̀ aṣòfin àpapọ̀. Olùdámọ̀ràn pàtàkì sí Ààrẹ lórí ìròyìn àti Ìpolongo, Femi Adesina sọ èyí fún àwọn oníròyìn lẹyìn ìpàdé tó wáyé ní Ọjọ́bọ̀ tí Ààrẹ…

Àwọn Òṣìṣẹ́ Ìrànlọ́wọ́ Tó Ní Idẹna Láti Kúrò Ní Tigray Ethiopia Tí Gbà Òmìnìra

Àwọn òṣìṣẹ́ ìrànlọ́wọ́ UN ní àgbègbè Ethiopia tó ni ìdènà láti jáde ní Tigray nigbati ìjà bẹ sílẹ̀, tí gbà òmìnìra lẹyìn ọsẹ púpọ̀ ní ìpamọ́. Ọkàn nínú àwọn olórí ni UN Martin Griffiths sọ lórí ẹrọ ayélujára rẹ pé “àwọn òṣìṣẹ́ náà ní…

Àwọn Ololufẹ Olùdijé Ààrẹ Ẹgbẹ́ Òṣèlú APC NÍ Ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́ Ṣé Iwọde Àtìlẹ́yìn Fún

Àìmọye àwọn alatilẹyìn fún olùdijé ipò Ààrẹ Ẹgbẹ́ òṣèlú All Progressives Congress (APC) Asíwájú Bola Ahmed Tinubu, ṣé ìpolongo ìbó káàkiri ìgboro ìlú Ìbàdàn, olú ìlú ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́, fún àwọn olùdijé Ààrẹ Tinubu/Shettima níbí ìdìbò…
button