Àjọ àgbábọ́ọ̀lù ilẹ̀ Áfíríkà tí sùn ifẹsẹwọnsẹ Kéjì láàrin Wydad Casablanca tí Morocco àti Enyimba FC tí Ilẹ̀ Nàìjíríà nínú ìdíje bọ́ọ̀lù Áfíríkà tí ń lọ lọ́wọ́ látí ọjọ́ kẹẹdọgbọn sí ọjọ́ kẹrindinlọgbọn oṣù kẹwàá.
Èyí ló wáyé lẹyìn ẹsùn pé àwọn aláṣẹ Ìlú Morocco ń gbé àwọn ìgbésẹ̀ tó burú láti bá inú àwọn àgbábọ́ọ̀lù Enyimba jẹ́ – èyí tó fá kí ẹgbẹ́ náà fí ẹsùn kàn wọ́n.
David Orji, Alàkóso ibanisọrọ tí ẹgbẹ́ Aba, sọ èyí nínú ọrọ kàn ní ìlú Èkó
Leave a Reply