Tí ìdùnnú tí ayọ̀ ní gbogbo àwọn ènìyàn wà nílùú Abeokuta, tó jẹ́ olu-ilu ìpínlẹ̀ Ogun, nígbà tí Ààrẹ orílẹ̀-èdè Nàìjíríà ṣe kéde ayẹyẹ eré ìdárayá ẹlẹ́ẹ̀kejìlélógún ní ìforígbárí, pẹ̀lú àwọn olóyè, àwọn olóṣèlú, àwọn ògbóǹtagí eré ìdárayá àtàwọn míì tí wọ́n ti rí ayẹyẹ náà.


Ààrẹ orílẹ̀-èdè Nàìjíríà, Bola Tinubu tí igbákejì Ààrẹ, Kashim Shettima, ṣójú fún níbí ayẹyẹ eré ìdárayá.


Ìdíje náà tí wọ́n fí ìsàmì rẹ̀ sọọ ‘Gateway 2024’, ní èrò láti ṣé agbega iṣọkan, dídára jùlọ ati ìwúrí orílẹ-èdè nípasẹ àwọn eré ìdárayá àti bí àwọn èèyàn jankan jankan tí tú jáde láti wà níbí ayẹyẹ naa.


Comments are closed.