Igbákejì Adarí Ilé Ìgbìmọ̀ Asòfin, Ọ̀gbẹ́ni Benjamin Kalu ti lu àwọn òsìṣẹ́ lọ́gọ ẹnu látàrí ipa tí wọn kó fún ìdàgbàsókè Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà
Nínú ọ̀rọ̀ rẹ̀ ní àyájọ́ Òsìsẹ́ tí àgbáyé, ti ọdún 2025, Kalu sàfihàn ìpinnu ìsèjọba Ààrẹ Bọla Tinubu láti mú ìgbéga bá àwọn òsìṣẹ́, papàá jùlọ bíbuwọ́lu àlékún owó òsìṣẹ́ tí ó kéré jùlọ
Ó pàrọwà sí ọmọ Naijiria láti ní ìfaradà, kí wọ́n sì se àtìlẹyìn fún ìsejọba Ààrẹ Tinubu, ó wá fi àrídájú hàn pé àtúntò tí ó ń lọ lọ́wọ́ yóò so èso rere fún Orílẹ̀-èdè