Alákòsóo Àjọ Ọmọ Ogun (COAS) Ọ̀gágun Taoreed Lagbaja ti pàrọwà sí àwọn ọmọ ogun láti máse kùnà nínú ojúse wọn, kí wọ́n sì siṣẹ́ dójú àmì
Ó sọ ọ̀rọ̀ náà níbi àsekágbá àpérò ìpín alákọ̀kọ́ọ́ ti ọdún 2024 èyí tí ó wáyé ní ọ́ọ́fìsì àpapọ̀ àjọ ọmọ ogun tí ó wà ní ìlú Abuja
Ọ̀gágun Lagbaja gbóríyìn fún àwọn ọmọ ológun Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà, papàá jùlọ àwọn adarí fún ojúse tí ó péye lásìkò tí Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà ń kojú ọ̀pọ̀lọpọ̀ ìsòro
Comments are closed.