Ìbásepọ̀ Yóò Wáyé Láàrin Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà Àti Bangladesh Lójúnà Àti Mú Ìgbòòrò Bá Ètò Ọ̀gbìn
Ìjọba Àpapọ̀ ti fi ìgbáradì rẹ̀ léde láti fi ọwọ́ sowọ́pọ̀ pẹ̀lú Bangladesh lórí ètò ọ̀gbìn ìgbàlódé lójúnà àti mú ìgbòòrò bá ètò ọ̀gbìn àti ìbásepọ̀ tí ó múná dóko láàrin Orílẹ̀-èdè méjéèjì náà.
Arábìnrin Anthonia Eremah ti ẹka ètò ọ̀gbìn àti ìdàgbàsókè ìgbèríko fún ìjọba àpapọ̀ ni ó fi ọ̀rọ̀ náà léde ni ọjọ́ Ajé , ní ìlú Abuja.
Ó fi àrídájú hàn pé, ìbásepọ̀ náà yóò mú kí oúnjẹ pọ̀ yanturu, ìpèsè iṣẹ́, àti bẹ́ẹ̀ bẹ́ẹ̀ lọ.
Leave a Reply