Take a fresh look at your lifestyle.

lẹ́yìn Ìnira, Ìdẹ̀kùn Lókù: Láìpẹ́ Jọjọ Ara Yóò Dẹ Mùtúmùwà- Ààrẹ Tinubu

0 169

 

Ààrẹ Bọla Ahmed Tinubu so pé òun kò se aláìmọ̀ pé nǹkan le koko fún àwọn ọmọ Nàìj́iríà látàrí yíyo ìrànwọ́ orí epo, Ó wá fi ọwọ́ sọ̀yà pé, láìpẹ́ àyípadà rere yóò débá Orílẹ̀-èdè wa.

 

Ó tún fi àrídájú hàn pé ìgbéga yóò dé bá Orílẹ̀-èdè Naijiria, sugbọn O pàrọwà si ọmọ Naijiria fun ìfaradà kí á le è jẹ ọrọ̀ lẹ́yìn ìlekoko náà.

 

Ààrẹ fi orọ naa lede nigba ti o sèpàdé pọ̀ pẹ̀lú àwọn gómìnà tẹ́lẹ̀rí ti ọdun 1999 ni ọ́ọ́fìsì Ààrẹ, ni ilu Abuja, níbití ó ti bèrè fún àtìleyìn wọn.

 

 

Leave a Reply

Your email address will not be published. Required fields are marked *

button