Adarí ilé -isẹ́ ikọ̀ ọmọ -ogun orílẹ̀ èdè Nàíjírìà sàbẹ̀wò si ibi ìgbáradì…
Ní ìtèsíwájú lórí ìrìn -àjo rẹ̀, adari ile-isẹ ọmọ ogun orilẹ ede Naijiria ọgagun Faruk Yahaya, ṣàbẹ̀wò ti se abẹwo sí ibùdó ìgbaradi awọn ọmọ ogun orilẹ ede yii to wa ni ní Falgore, Kano, níbití ikọ ọmọ ogun orilẹ…