Nàìjíríà, Bulgaria yóò túnbọ̀ fìdí ètò ẹ̀kọ́ ààrin wọn múlẹ̀ si
Mínísítà fún ètò Ẹ̀kọ́, Ọ̀jọ̀gbọ́n Tahir Mamman, ti sọ pé Nàìjíríà ti ṣetán láti túnbọ̀ fìdí àjọṣepọ̀ pẹ̀lú orílẹ̀-èdè Bulgaria múlẹ̀ ní abala ètò ẹ̀kọ́.
Minisita naa wa pinnu pe wọn yoo ṣe eto isọdọtun adehun…