Asòfin ṣàpéjúwe ìyanṣélódì ẹgbẹ́ olùkọ́ni fáfítì gẹ́gẹ́ bí ìtìjú fórílẹ̀-èdè
Ọmọ ẹgbẹ́ Aṣòfin àpapọ̀ orílẹ̀-èdè Nàìjíríà, Hon Bùsáyọ̀ Olúwọlé Ọ̀ké ti ṣàpéjúwe ìdaṣẹ́sílẹ̀ àwọn òṣìṣẹ́ ilé-ẹ̀kọ́ gíga orílẹ̀-èdè lábẹ́ agbòòrùn (ASUU), gẹ́gẹ́ bí ìtìjú fún orílẹ̀-èdè.
Ninu…