Al-Shabaab sọ pé òun ló wà nídìí ìkọlù apànìyàn tó ṣẹlẹ̀ ní Ibùdó AU ní Sòmálíà
Àwọn ajagun Al-Shabaab ti yabo ilé-iṣẹ́ ìṣọ̀kan Áfíríkà kan ní Sòmálíà pẹ̀lú ìbọn àti ibẹjadi ní ọjọ́ ìṣégun,ní èyí tí ó fa ìyìnbọn lura tí ó pa àwọn olùpèsè alààfíà Burundi.
Ọgágun ọmọ ogun Burundi…