Take a fresh look at your lifestyle.

Àsìkò Ramadan: Gómìnà ìpínlẹ̀ Gombe Pé Fun Ìṣọ̀kan nínú Ẹ̀sìn Àti Ádùrá.

Gẹ́gẹ́ bí ati mọ̀ pé Ramadan bẹ̀rẹ̀ lo ní , ọjọ́ kọkànlá oṣù kẹta ọdún 2024. Alága fún ẹgbẹ́ àwọn Gómìnà jákèjádò, Gómìnà ìpínlẹ̀ Gombe Muhammadu Inuwa Yahaya, ti rọ àwọn Mùsùlùmí káàkiri àgbáyé láti gbàdúrà fún ìsọ̀kan àti idẹra…

Àwọn Tó N ṣe Ìwádìí Pé Fún Iṣé To Ta Yọ Fún Àwọn Ọ̀dọ́ Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà.

Ẹgbẹ́ àwọn tó n ṣe ìwádìí ti gba ijoba, àwọn Aláàdáni pẹlu àwọn tọ́rọ̀ kan lámọ̀ràn láti pèsè iṣé to tà yọ fún àwọn ọ̀dọ́ Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà. Wọn ní lati ipasẹ̀ ìdánilékòó ati àtìlẹ́yìn owó fún àwọn ọ̀dọ́ Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà ẹyin yóò mú…

Àwọn oníròyìn obìnrin ṣàjọyọ̀ Àyájọ́ Àwọn obìnrin Káríayé

Àwọn ọmọ ẹgbẹ́ àwọn obìnrin Akọ̀ròyìn ní Nàìjíríà (NAWOJ, ti ikọ̀ FCT ti ró àwọn obìnrin tó ju igba lágbára lọ ní ààfin Nga’Kupi Sa’peyi, ní Garki Village, Abuja, gẹ́gẹ́ bí ayẹyẹ láti ṣàmì Àyájọ́ àwọn obìnrin…

Ìpínlẹ̀ Kwara : Ẹgbẹ́ ra fọ́ọ̀mù JAMB Fún àwọn ẹgbẹ̀rún méjì akẹ́kọ̀ọ́ tí kò lówó láti…

Ẹgbẹ́ Amana ti ra fọ́ọ̀mù ìdánwò láti wọ ilé ìwé gíga Fáfítì (JAMB) Fún àwọn ẹgbẹ̀rún méjì akẹ́kọ̀ọ́ tí kò lówó láti ràá ní ìpínlẹ̀ Kwara, Àríwá Àringbùngbùn Nàìjíríà. Alaṣẹ Adari National Institute…

Ìṣèfilọ́lẹ̀ Isẹ́ Àkànṣe: Ìpínlẹ̀ Niger yóò gbàlejò ààrẹ Tinubu

Ìjọba ìpínlẹ̀ Niger ní Àríwá Àringbùngbùn Nàìjíríà ti parí ìpalẹ̀mọ́ fún ìṣàbẹ̀wò ààrẹ Ahmed Bọla Tinubu ní ìrọ̀rùn, fún Ìṣèfilọ́lẹ̀ ẹ̀rọ ọhun ọ̀gbìn tí wọ́n rà, tí ó tó Bílíọ́nù Náírà, nínú àwọn…

Akọ̀wé àgbà Ilé Aṣòfin Èkó kìlọ̀ fún àwọn òṣìṣẹ̀ láti má ṣe fi àwọn ìròyìn àṣírí nípa iṣẹ́ jáde

Akọ̀wé àgbà Ilé Aṣòfin Ìpínlẹ̀ Èkó, Amòfin Ọlálékan Ọ̀náfẹ̀kọ̀ ti ṣe kìlọ̀ kìlọ̀ fún àwọn òṣìṣẹ̀ Ilé Aṣòfin náà àti ti Ìgbìmọ̀ Aṣàkóso Ilé Aṣòfin náà láti má ṣe fi àwọn ìròyìn ẹlẹ́nu iṣẹ́ nípa Ilé Aṣòfin náà síta láìgba àṣẹ. Ọ̀nàfẹ̀kọ̀…
button