Browsing Category
ÌRÒYÌN ÈTÒ Ọ̀GÌN ÀTI ÀYÍKÁ
Ìmọ́tótó Ni Ó L e è Ṣẹ́gun Àrùn Gbogbo: Akọ́ṣémọṣẹ́ Pè Fún Ìmótótó Láti Kojú…
Akọ́sẹ́mọṣẹ́ Nípa Ètò Ìlera, Arábìnrin Veronica Augustine ti pàrọwà sí gbogbo ọmọ Nàìjíríà láti mú ìmọ́tótó ní ọ̀kúkúdùn lójúnà àti kojú ìsòro gbogbo àrùn
Ó sọ ọ̀rọ̀ náà ní ìlú Abuja, ní ọjọ́…
Ìjọba Ní Láti Fi Kún Ìpèsè Ohun Èèlò Gbogbo Fún Agbẹ̀- Akọ́sẹ́mọsẹ́
Àgbẹ̀ akọ́sẹ́mọsẹ́, ọgbẹni Titilayo Adebanjo ti rọ ìjọba ìpínlẹ̀ àti apapọ̀ lati fi kun oye isuna ọdọọdún àgbẹ láti jẹ ki ounjẹ sunwa bọ̀ ni Nàìjíríà.
Adebanjo, to jẹ oga ile iṣẹ Agrorebirth ló gba ijọba niyanju yìí nigbati o n…
Ilé -Iṣẹ́ Tí Ó Wà Ní Títìpa Látàrí Bíba Afẹ́fẹ́ Jẹ́ Ní Ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́ Ti Bẹ̀rẹ̀ Iṣẹ́…
Ìjọba ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́ ti sí ilé isẹ́ tí ó ń lo táyà gẹ́gẹ́ bí ohun èlò ní ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́, èyí tí ó ti wà ní títìpa tẹ́lẹ̀rí látàrí bíba afẹ́fẹ́ jẹ́ àti kíkó ìnira bá àwùjọ
Kọmísọ́nà fún…
Ìjọba Ìpínlẹ̀ Enugu: ìṣòwò Ọgbà Oko Ń lá Ni A Ń Ṣe O, Ki Ṣe Owó Màálù.
Ìjọba Ìpínlẹ̀ Enugu sọ wí pé àwọn kò ṣe owó RUGA èyí tí o nise pẹ̀lú owó Maalu, bikòṣe owó Ranch èyí tó nisè pẹ̀lú ọgbà àjàrà nlá ti àwọn ènìyàn yóò fi gbin nkán ọgbin sí ati ṣinṣin nkan osin
Nínú atẹjade kan láti ọwọ́ Kọmísọ́nà fún…
Ìjọba Ìpínlẹ̀ Èkó Se Ìdánilẹ́kọ̀ọ́ Lórí Ìmọ́tótó Oúnjẹ Fún Àwọn Ẹ̀ẹ́dẹ́gbẹ̀ta…
Ìjọba ìpínlẹ̀ Eko ti pinnu láti tẹ̀síwájú lórí ìdánilẹ́kọ̀ọ́ fún àwọn olùtajà lórí ìmọ́tótó, ìpamọ́ ati síṣe akẹ́tọ̀ọ́ àwọn ohun jíjẹ lójúnà àti mú kí oúnjẹ pọ̀ yanturu
Arábìnrin Abisọla Olusanya tí…
Ilé Ìfowópamọ́ Ti Mùsùlùmí Ti Fi Ìgbáradì Rẹ̀ Léde Láti Se Ìrànlọ́wọ́ Fún…
Ilé ìfowópamọ́ tí ó jẹ́ tí àwọn ẹlẹ́sìn Mùsùlùmí ti fi ìgbáradì rẹ̀ léde láti se àtìlẹyìn fún Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà fún ìdàgbàsókè tí ó péye
Adarí ilé ìfowópamọ́ náà, Ọ̀gbẹ́ni Javed…
Àsọyépọ̀ Wáyé Láàrin Àwọn Ìpínlẹ̀ Ní Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà Láti Mú Àlékún Bá…
Ìjọba ìpínlẹ̀ Èkó ti bẹ̀rẹ̀ ìjíròrò pẹ̀lú ìpínlẹ̀ Niger àti Kwara láti mú ìgbòòrò bá ìpèsè oúnjẹ láàrin àwọn ìpínlẹ̀ náà nínú àgbékalẹ̀ kan tí ó wáyé ní ìpínlẹ̀ Èkó
Ìgbésẹ̀ náà wáyé…
Àjọ AFAN: Ìpínlẹ̀ Enugu Yóò Gbádùn Ìpèsè Ẹ̀gẹ́ Yanturu
Alága àjọ , All Farmers Association of Nigeria (AFAN) ni ìpínlẹ̀ Enugu, ọ̀gbẹ́ni Romanus Eze, ti sọ pé ìrètí wà fún ìpèsè ẹ̀gẹ́ yanturu ninu ọdún yìí.
Ọgbẹni Eze sọ eyi níbi ìfòròwánilẹ́nuwò ni ilu Enugu ni ọjọ Ọjọ́rú. O sọ pe ọpọ…
Ìjọba Àpapọ̀ Àti Ìpínlẹ Kebbi Ti Parí Ètò Láti Mú Ìgbòòrò Bá Ètò Ọ̀gbìn Èyí Tí…
Ìjọba àpapọ̀ àti Ìpínlẹ̀ Kebbi ti gbé ìgbésẹ̀ akin láti mú ìgbòòrò bá ètò ọ̀gbìn èyí tí yóò mú àdíkù bà ọ̀wọ́ngógó oúnjẹ, tí oúnjẹ yóò sì wà lọ́pọ̀ yanturu
Mínísítà Fún Ètò Ọ̀gbìn àti…
Ìsẹ̀lẹ̀ Idagiri Ẹgbẹ̀rún Kan-lé-lẹ́ẹ̀dẹ́ẹ́gbẹ̀ta Ní Ó Wáyé Ní Ìpínlẹ̀ Eko Nínú Ọdún…
Àjọ tí ó ń mójútó ìsẹ̀lẹ̀ pàjáwìrì ní ìpínlẹ̀ Eko, (LASEMA) ti sọ pé, ó tó ìsẹ̀lẹ̀ ẹgbẹ̀rún kan lé lẹ́ẹ̀dẹ́ẹ́gbẹ̀ta tí ó wáyé láàrin ọjọ́ kíní osù kíní ọdún 2023 sí ọjọ́ kọkànlélọ́gbọ̀n osù kejìlá…