Ó ti lé ní mílíọ̀nù mẹ́ta ọmọ orílẹ̀ èdè Nàíjíríà, tó ti gba abẹ́rẹ́ àjẹsára COVID-19 (3,938,945) ni kaakiri gbogbo ipinlẹ to wa ni jake-jado orilẹ ede Naijiria.
Eleyii jẹyọ ninu atẹjade kan ti awọn aosju -sofin orilẹ ede Naijiria gbe wa si ile igbimọ aosju-sofin ti ilẹ Afirika, iyẹn ECOWAS Parliament.
ọkan ninu ọmọ ile igbimọ asofin Lynda Chuba Ikpeazu, lo gbe atẹjade ọhun wa si ile-igbimọ asofin ti ilẹ Afirika.
Leave a Reply