Aarẹ Muhammadu Buhari ti fi ara-ilu Naijiria lọkan balẹ pẹ isẹ akansẹ ori afara keji to wa ni Niger, ipinlẹ Eko si ilu Ibadan ti ijọba apapọ dawọ le ni wọn yoo pari ki ijọba yii to pari saa keji ti wọn gùnlé.
Aarẹ sọrọ yii lọjọ Aje lasiko ti wọn n se igbeyẹwo awọn aseyọri isẹ akanse ti ijọba rẹ ti se lati igba ti o ti wa n i ijọba.
ṣalaye bi inu oun se dun si awọn minisita to n jabọ yii lasiko ti Igbimọ ijọba apapọ n salaye aseyọri ti wọn ti se lati ọdun meji sẹyin ti wọn ti ninu ijọba rẹ.
Aarẹ tun tẹsiwaju pe ọpọlọpọ aseyọri miran ni ijọba rẹ ti se paapaa julọ nipa ọkọ oju irin lorilẹ ede Naijiria.
O tun sọ pe ijọba rẹ ko ni kaare lati tun tẹpẹlẹ mọ eto aabo, ẹka amusagbara ati idagbasoke lori ironilagbara fun awọn ọdọ.
Bankọle ati Olufunmi
Leave a Reply