Take a fresh look at your lifestyle.

Àjọ WHO Gbóríyìn Fún Ìjọba Ìpínlẹ̀ Kano Lórí Dí Dènà Àìsàn Imú.

0 101

Àjọ ìlera Làgbáyé (WHO) tí Gbóríyìn fún ìjọba ìpínlẹ̀ Kano fún àpẹrẹ réré tó fi hàn àti àtìlẹ́yìn rẹ lórí ọ̀rọ̀ ìlera, nípa di dèna àìsàn to n ba imú po.

Aṣojú àjọ WHO ni Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà Walter Kazad sọ wí pé ìpínlẹ̀ náà ti fí àpẹrẹ réré hàn nípa ìlera lórí ilu náà.

Ó sọ èyí nígbà ẹgbẹ́ Global Fund ṣe ìbẹ̀wò sí Gómìnà ìpínlẹ̀ náà Abba Yusuf ni ilé ìjọba ni ọjọ́rú.

O wà rọ gbogbo awọn ìpínlẹ̀ tó kún láti wo àwòkọ́ṣe ìpínlẹ̀ náà fún ìdàgbàsókè Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà.

Gómìnà Yusuf sọ fún ilẹ iṣé Global Fund wí pé ìjọba ìpínlẹ̀ òun yóò tẹ̀sìwájú láti rí wí ìpínlẹ̀ náà wà nínú àláfíà pípé

Leave A Reply

Your email address will not be published.