Take a fresh look at your lifestyle.

Mínísítà Olú-ìlú Nàìjíríà Gbèrò Látí Máà Ló Owó Tí Ilé-iṣẹ́ Náà Pá Fún Àwọn Iṣẹ́ Àkànṣe

Ọlálékan Ọ̀rẹ́núgà

0 226

Mínísítà tí Olúìlú Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà, Abuja, Nyesom Wike tí kéde pé láti àkókò yíì, àwọn owó tí wọ́n bá pá lábẹ́lé (IGR) ní wọ́n yóò máa ló fún àwọn iṣẹ́ àkànṣe kàn.

Mínísítà náà sọ làkókò tó ń ṣàlàyé àwọn ìgbésẹ̀ akin látí ṣé àtúnṣe àwọn ipò tí Olúìlú náà wà, èyí tí kò ní fí ayé gbá ìgbẹ́kẹ̀lé ìpèsè ìṣúná tí ìjọba àpapọ̀.

Nítorí bẹ́ẹ̀, Ó rọ́ àwọn olùgbé látí yàgò fún àìsàn owó-ilẹ̀ àti owó-orí déédé sí àpò ìjọba. Ó tún fí kún pé kòní sí Ìgbàlààyé fún á ń ló ipò tàbí imọnìyàn fún ẹnikẹ́ni tó bá kùnà láti ṣé ojúṣe rẹ̀.

Nígbàtí Ó ń sọ̀rọ̀ lórí ipá tí ètò ọrọ̀-ajé, Mínísítà náà sọ pé gbèsè àwọn ènìyàn tó látí ṣé ìṣúná ìnáwó tí Abuja fún ọdún mẹwàá.

Mínísítà náà wà ló ànfààní yìí láti tókasí 825m Náírà owó àwọn onílè tí ìjọba gbà lójúnà iṣẹ́ àtúnṣe fún ìdàgbàsókè ojú-ọnà ọkọ Òfurufú Kejì tí Abuja. Nítorí bẹ́ẹ̀, Ó pàṣẹ fún Àkọwé àgbà tí Ilé-iṣẹ́ náà láti fún olúkúlùkù ní ẹtọ́ wọ́n ṣáájú òpin Ọsẹ yìí kí iṣẹ́ lè bẹ̀rẹ̀ ní pẹrẹwú.

Leave A Reply

Your email address will not be published.