Gómìnà ìpínlẹ̀ Niger, Abubakar Sani Bello ti pe àwọn Mùsùlùmí láti lò àkókò oṣù awé láti fi bẹ Ọlọrun fún ọpọ ìbùkún ní Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà
Gómìnà sọ èyí nínú àtẹjáde kan ti agbẹnusọ rẹ̀ Mary Noel Berje ka wí pé ádùrá irẹpọ àti àlàáfíà ni ko pọju lakoko oṣù awé yìí.
Ó rọ àwọn mùsùlùmí lati tẹ̀lé ofin àti ìlànà Ọlọrun nínú oṣù awé yìí fún ọpọ àlàáfíà àti ìmísí ọlọrun.
Leave a Reply