Take a fresh look at your lifestyle.

Ààrẹ Buhari Yan Alága Tuntun Fún Ìgbìmọ̀ Ohun Tó Niye Lórí.

0 219

Ààrẹ Muhammadu Buhari tí yan Ọgbẹni Osita Anthony Abolama gẹ́gẹ́ bí alága tuntun fún ìgbìmò ohun tó níye lórí.

 

Nínú àtẹ̀ jáde kan láti ọwọ́ Mínísítà fún káràkátà, Ifedayo Sayo, ó ní ipò tuntun náà tó iṣẹ rẹ bẹrẹ lati oṣù kẹjọ o 2022 jẹ́ àtúnyàn sípò gẹ́gẹ́ bí elekeji gégé bí alága fún ẹgbẹ́ nàá

Leave a Reply

Your email address will not be published. Required fields are marked *

button