Take a fresh look at your lifestyle.

Mínísítà yóò ṣojúu ààrẹ Bùhárí ní COP27 ní Egypt

Eyitayọ Fauziat Oyetunji

0 138

Ààrẹ Nàìjíríà, Mùhámmádù Bùhárí ti  yan Mínísítà  àyíká, Ọ̀gbẹ́ni  Mohammed Abdullahi láti ṣojú rẹ̀ gẹ́gẹ́ bí adarí aṣojú Nàìjíríà sí àpèjọ àjọ ìṣọ̀kan àgbáyé.

Àpèjọ lórí ìyípadà ojú-ọjọ́ náà yóò wáyé ní Sharm El Sheikh,ní Egypt, láti ọjọ́ kẹfà sí ọjọ́ kejìdín-lógún,oṣù Kọkànlá,ọdún 2022.

Abdullahi yóò ṣojú Ààrẹ ní ìpele gíga tí yóò sì tún ṣe ìjábọ̀  orílẹ̀-èdè Nàìjíríà níbi ìjíròrò Cop27, yóò tún sẹ ìpàdé pẹ̀lú ẹgbẹ́ lórí ètò ìyípadà iná Nàìjíríà láàrin àwọn ìpinnu mìíràn.

Leave A Reply

Your email address will not be published.