Ilé Ẹjọ́ Òṣìṣẹ́ tí orilẹ́-èdè ni ìlú Abuja, tí pàṣẹ wípé kí ẹgbẹ́ àwọn olùkọ tí Fásítì orílẹ̀-èdè Nàìjíríà dáwọ́ ìyànsẹ́lódí tó nlọ lọ́wọ́ láti oṣù keje sẹyìn.
Mínísítà fún àwọn òṣìṣẹ́ and gbigba ni siṣẹ , Onísègùn Chris Ngige,ti sojú ìjọba Nàìjíríà, tí pẹ ejò láti wá ìyanú sí ọrọ Ìyànsẹ́lódí to nlọ lọwọ pẹlú ẹgbẹ́ ASUU.
Leave a Reply