Take a fresh look at your lifestyle.

Asòfin ṣàpéjúwe ìyanṣélódì ẹgbẹ́ olùkọ́ni fáfítì gẹ́gẹ́ bí ìtìjú fórílẹ̀-èdè

Eyitayọ Fauziat Oyetunji

0 250

Ọmọ ẹgbẹ́ Aṣòfin àpapọ̀ orílẹ̀-èdè Nàìjíríà, Hon Bùsáyọ̀ Olúwọlé Ọ̀ké ti ṣàpéjúwe ìdaṣẹ́sílẹ̀  àwọn òṣìṣẹ́ ilé-ẹ̀kọ́ gíga orílẹ̀-èdè  lábẹ́ agbòòrùn (ASUU), gẹ́gẹ́ bí ìtìjú fún orílẹ̀-èdè.

Ninu atẹjade kan ti aṣofin naa fi sita nilu Abuja, o ni wahala to waye laarin ASUU ati Ijọba apapọ to mu ki wọn ti awọn ile iwe giga orilẹ-ede pa fun ọpọlọpọ oṣu sẹyin, ti ko si lojutu yẹ ki o jẹ nkan ti yoo jẹ  gbogbo eniyan logun

Aṣofin naa wa da laba pe ki Ile-igbimọ Aṣofin Orilẹ-ede  ti o lọ fun isinmi ọdọọdun lọwọlọwọ bayii, yẹ ki o tun ṣe apejọ lẹsẹkẹsẹ lati pari idaṣẹsilẹ naa laisi idaduro kankan.

 

Leave a Reply

Your email address will not be published. Required fields are marked *

button