Orílẹ̀ èdè Nàíjíríà ti ní òun yóò kúrò láti máa jẹ́ ọmọ ẹgbẹ́ ajọ ilẹ alawọ dúdú iyẹn , Economic Community of West African States (ECOWAS).
Ipe yii waye latari bi àwọn adarí àjọ ohun se ń se ojú saaju si bi wọn se n gba awọn mọlẹbi ati ibatan wọn sẹnu isẹ .
Asoju orilẹ ede Naijiria ní ile igbimọ asofin ní ECOWAS tó wà nílùú Abuja, ti o tun jẹ igbakeji adari ilé igbimọ asofin ti ajọ ECOWAS, Ahmed Idris Wase lo sọrọ nibi ipade ti ajọ ile igibmọ asofin ECOWAS se lọdun 2022. pé, ó tí di dandan ki orilẹ ede Naijiria se atunyẹwo lori ipò rẹ̀ ati jíjẹ́ ọmọ ẹgbẹ́ ECOWAS.
Leave a Reply