Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà àti Orílẹ̀-èdè Portugal ti ṣètò láti fọwọ́ sí ìwé àdéhùn mẹ́wàá àti ìwé òye lakòókò ìbẹ̀wò Ààrẹ Muhammadu Buhari sí Orílẹ̀-èdè Europe.
Ààrẹ Buhari sọ èyí ní ọjọ́bọ̀, ní àpèjọ àpapọ̀ pẹ̀lú Ààrẹ Marcela Rebelo de Sousa ti Orílẹ̀-èdè Portugal.
Ọláyinká Akíntọ́lá.
Leave a Reply