Take a fresh look at your lifestyle.

Adarí ilé -isẹ́ ikọ̀ ọmọ -ogun orílẹ̀ èdè Nàíjírìà sàbẹ̀wò si ibi ìgbáradì ìgbanísíṣẹ́, ní Ibùdó Falgore

Eyitayọ Fauziat Oyetunji

0 315

Ní ìtèsíwájú lórí ìrìn -àjo rẹ̀, adari ile-isẹ ọmọ ogun orilẹ ede Naijiria  ọgagun  Faruk Yahaya, ṣàbẹ̀wò  ti se abẹwo sí ibùdó ìgbaradi awọn ọmọ ogun orilẹ ede yii  to wa ni  ní Falgore, Kano, níbití ikọ ọmọ ogun orilẹ ede yii ti ń gbaradì fún ìdánwò  lati gba wọn si isẹ́ ológun.

Igbaradi, eyi ti o jẹ apakan lara akitiyan ile-isẹ ologun orilẹ ede  Naijiria ki wọn to bẹrẹ isẹ ologun ni ẹkunrẹrẹ ,ni Falgore, lati jẹ ki awọn oṣiṣe tuntun mọ iṣẹ ti wọn gba ati bi asiko  oju ọjọ ṣe n ri, lakoko idanilẹkọọ wọn:

Adari ile-isẹ ikọ ọmọ ogun orilẹ ede Naijiria , wa  rọ ikọ ọmọ orilẹ ede  yii lati gbaradi fun ipenija to wa niwaju wọn , ni eyi ti o bẹrẹ  ni , ọjọ keje, Oṣu Kẹjọ, ọdun 2021.

O tun tẹsiwaju pe   Ile -iṣẹ ọmọ ogun yoo  pese awọn ohun elo  ati awọn amayederun miran, ti yoo wulo fun  aṣeyọri ayẹwo igbanisiṣẹ ti n wọn n se.

 

 

Leave a Reply

Your email address will not be published. Required fields are marked *

button