Take a fresh look at your lifestyle.

Ilé-iṣẹ́ tí ó ń tẹ owó ní orílẹ́-èdè Nàìjíríà fi gbegedé sórí títẹ owó jáde

Eyitayọ Fauziat Oyetunji

0 280

Olùdarí Alákóso, ilé-iṣẹ́ ìtẹwó ní orílẹ̀ èdè Nàìjíríà, NSPMC, Abbas Umar Masanawa sọ pé, ilé-iṣẹ́ ọ̀hún ti ṣàṣeyọrí tó lámì nínú títẹ  owó síta ní orílẹ̀-èdè Naijiria.

Ile-iṣẹ naa tun ni agbara  lati tẹ  owo  nina fun  o kere ju, awọn orilẹ-ede Iwọ-oorun Afirika marun miiran.

Oludari Alakoso, NSPMC kede eyi nigba ti o ṣe  abẹwo si  Alaga  ajó to n gbogun ti sise owo ilu kúmọ-kùmọ lorilé ede Naijiriati inawo, EFCC, Abdulrasheed Bawa ni ilu Abuja, Naijiria.

O ṣalaye pe, ile-iṣẹ naa ti kuro ni ṣiṣatilẹyin fun owo isuna nikan, o ti n mowo wọle,ti o si tun n pese iṣẹ aje fun awọn ọmọ orilẹ ede  Naijiria.

 

Leave a Reply

Your email address will not be published. Required fields are marked *

button