Ìjọba orílẹ̀ èdè Nàíjíríà ti ní ohun yóò mú ètò ààbò le ní àwọn ojú àlà tó wà káàkiri orílẹ̀ èdè yìí láti leè dènà ààrùn COVID -19 tuntun tó tún fẹ́ jẹyọ.
Alaga igbmọ ijọba apapọ to n mojuto gbigbogun ti aarun COVID-19 lorilẹ ede Naijiria , Boss Mustapha lo sọ eleyii niluu Abuja,lasiko ifọwọwanilẹniwo pẹlu awọn akọroyin.
” Ni awọn ọsẹ to kọja ni a kede awọn igbesẹ ti a n gbe nipa awọn arinrirnajo ti wọn wa lati orilẹ ede Brazil, Turkey ati India. Eyi ni lati dena aarun COVID-19 tuntun miran ti o tun jẹyọ bayii.
Leave a Reply