Take a fresh look at your lifestyle.

Nàíjíríà kò ní jẹ́ kí wọ́n kó ààrùn COVID-19 tuntun wọ́lé nípa gbígba àlà wọn

0 259

Ìjọba orílẹ̀ èdè Nàíjíríà ti ní ohun yóò mú ètò ààbò le ní àwọn ojú àlà tó wà káàkiri orílẹ̀ èdè yìí láti leè dènà ààrùn COVID -19 tuntun  tó tún fẹ́ jẹyọ.

Alaga igbmọ ijọba apapọ to n mojuto gbigbogun ti aarun COVID-19 lorilẹ ede Naijiria , Boss Mustapha lo sọ eleyii niluu Abuja,lasiko ifọwọwanilẹniwo pẹlu awọn akọroyin.

Ni   awọn ọsẹ to kọja ni a kede  awọn  igbesẹ ti a n gbe nipa awọn arinrirnajo ti wọn wa lati orilẹ ede Brazil, Turkey ati India. Eyi ni lati dena aarun COVID-19 tuntun miran ti o tun jẹyọ bayii.

Leave a Reply

Your email address will not be published. Required fields are marked *

button