Abẹnugan ilé ìgbìmọ̀ asòfin ,Ahmad Lawan ti rọ gbogbo àwọn adarí tí wọ́n jẹ́ ọmọ orílẹ̀ èdè Nàíjíríà láti máa sàánú àwọn àtìpó, ti ogun lé kúrò nílùú wọn,.
Asofin Lawan, sọrọ yii lọjọ Ẹti lasiko ti ikọ awọn asofin lọ si Wasa niluu Abuja, ni Gusu orilẹ ede Naijiria fun ajọyọ ayẹyẹ ọdun keji ti awọn asofin ti lò.
Asoju igbimọ asofin tun fun awọn atipo ọhun ni ẹbun owó miliọnu mẹwaa naira pẹlu ounjẹ ati awọn ohun elo míràn .
Leave a Reply