Ààrẹ Muhammadu Buhari ti fọwọ́sí àtúnse ìlànà ètò ojú ọjọ́ fún orílẹ̀ èdè Nàíjíríà.
Minisita fún ètò àyíká , ọmọwe Muhammad Mahomod tun sọ pe eto ilana tuntun yii yoo tun ni “Adehun ti aarẹ Muhammadu Buhari fọwọsi lọdun 2015 ní Paris, yoo wa ninu atunṣe tuntun ọhun , ni eyi to ni ṣe pẹlu ojú ọjọ́.”
Mahomodtun sọ pe eto ilana tuntutn fur oju ọjọ yii yoo bẹ̀rẹ̀ lọdun 2021 sí ọdun 2030.
Minisita wa dupẹ lọwọ aarẹ bo sẹ fọwọsi eto ilana fun ojú ọjọ́ , ni eyi to wa ni ibamu ilana ajọ agbaye.
Leave a Reply