Àwọn ènìyàn márùndínláàdọ́ta tún ti ní Corona lórílẹ̀ èdè Nàíjíríà bayii, ni eyi to ti jẹ ki iye awọn to ni COVID-19 jẹ́ ẹgbàáta-le-ni-ọ̀kẹ́-mẹ̀jọ-le-ni-ọ̀kan-le-ni-àádọ́wá(166,191).
Gẹgẹ bi ajo to n gbogun ti ajakalẹ aarun lorilẹ ede Naijiria , NCDC se kede rẹ lori ẹrọ Twitter wọn pe awọn ipinlẹ ti aarun naa gbe jẹyọ ni :
“Lagos-27 Rivers-14 Kaduna-2 Jigawa-1 Ekiti-1.”
Bakan naa, iye awọn ti o ti gba iwosan jẹ, ẹgbàáta-le-ni-ọ̀kẹ́-mẹ̀jọ-le-ni-ọ̀kan-le-ni-àádọ́wá (156,535) nigba ti iye awọn ti o ti padanu ẹmi wọn jẹ́ ọ̀kan-din-ni-ojì-din-ni-ẹ̀ẹ́dẹ́gbẹ́ọ̀kànlá (2,071).
Leave a Reply