Ọ̀gágun Farouk Yahaya di adarí tuntun fún ilé-isẹ́ ológun orílẹ̀ èdè Nàíjíríà
Ademọla Adepọju
Ààrẹ orílẹ̀ èdè Nàíjíríà , Muhammadu Buhari ti yan ọ̀gágun Farouk Yahaya gẹgẹ bi i adarí tuntun fún ilé-isẹ́ ológun,orílẹ̀ èdè Nàíjíríà láti rọ́pò olóògb́e ọ̀gágun Ibrahim Attahiru ti o padanu ẹmi rẹ̀ nínú ìjàḿbà ọkọ̀ bàálù tó wáyé́ ní ìpínlẹ̀ Kaduna lọ́sẹ̀ tó kọjá .
Leave a Reply