Ààrẹ orìlẹ́ èdè Nàíjíríà , Muhammadu Buhari ti ní ohun tó bá dé bá ojú ti dé bá imú, nítorì náà, wàhálà tó bá n sẹlẹ̀ lórílẹ̀ èdè Libya, di dandan kí ó kan orìlẹ́ èdè Naijiria, nítorí pé ́ orìlẹ́ èdè Chad ati Niger tí wọ́n súnmọ́ orìlẹ́ èdè Naijiria bi isan ọrùn mú àlà pẹ̀lú orìlẹ́ èdè Libya.
Aarẹ sọrọ yii lasiko to n tẹwọgba alaga igbimọ ijọba ti orilẹ ede Libya,Mohammed Younis Menfi, lọjọRu, niluu Abuja.
Mohammed Younis Menfi naa tun sọ pe, nibayii , awọn ti ni ij,oba kan lorilẹ ede Libya ati pe awọn ko ni pẹ bẹrẹ eto idibo laipẹ.
O tẹsiwaju pe orilẹ ede Naijiria ati Libay jọ ni itan iwasẹ kan naa ati awọn ohun alumọọni bi i epo rọbi, ohun ọgbin ati bẹẹbẹẹ lọ.
Leave a Reply