Covid-19: Àwọn ènìyàn méjìdínláàdọ̀ta míràn tun tí ní ààrùn lórílẹ̀ èdè Nàíjíríà
Ademọla Adepọju
Àwọn ènìyàn mọ́kàndínláàdọ̀ta míràn tun tí ní ààrùn Corona lórílẹ̀ èdè Nàíjíríà bayii.. Ni bayii iye awọn to ti ni aarun COVID ti jẹ ẹgbàáta-le -ni -ọ̀kẹ́- mẹ̀jọ-leni meérinlá-din-ni -àádọ́jọ (166,146) nigba ti awọn ti eniyan ti iye wọn jẹ ẹ̀ẹ́dẹ́gbàrin-le-ni-ọ̀kẹ́-mèje-abo -din- ni -ọ̀kan-din-ni-ojì -din -ni -ẹ̀ẹ́dẹ́gbẹ́ta ( 156,529 ) ti gba iwosan.A won eniyan ti o ti padanu ẹ̀mí wọn jẹ́ (2,071)
Awọn ipinlẹ ti aarun COVID-19 ti jẹyọ ni ; Lagos-22, Rivers-11, Enugu-11, Kaduna-2, FCT-1 ati Gombe-1.
48 new cases of #COVID19Nigeria;
Lagos-22
Rivers-11
Enugu-11
Kaduna-2
FCT-1
Gombe-1166,146 confirmed
156,529 discharged
2,071 deaths pic.twitter.com/Q74EIMUPjW— NCDC (@NCDCgov) May 26, 2021
Leave a Reply